Home News Bọlanle Aliyu: N kò Nílò Bàbá Ìsàlẹ̀ Láti Di Gómìnà Ipinlẹ Ọyọ

Bọlanle Aliyu: N kò Nílò Bàbá Ìsàlẹ̀ Láti Di Gómìnà Ipinlẹ Ọyọ

2108
0

Ọmọbọlanle Aṣabi Sarumi aya Aliyu ni obinrin akọkọ ti yoo jade lati du ipo gomina nipinlẹ Ọyọ.

Aliyu ni awọn obinrin to n gbe awọn ọkunrin de ipo giga lati ọdun gbọọrọ naa lẹtọ lati du ipo oselu, ki wọn si ri atilẹyin awọn ọkunrin yii.

Google search engine

O wa gba awọn akẹẹgbẹ lobinrin nimọran lati ṣe atilẹyin fawọn obinrin ẹlẹgbẹ wọn, kawọn obinrin lee ko ida marundinlogoji ti awujọ agbaye ni o yẹ ki wọn ni ninu oselu sise.

Previous articleOyo 2019: Oke-Ogun APC Leaders Commend Ayandele Over Statewide Consultation
Next articleOlubadan Reveals Plans For 90th Birthday Celebration, Appoints Ex-Minister C’tee Chair

LEAVE A REPLY

Please enter your comment!
Please enter your name here